Postagens

Mostrando postagens de janeiro, 2023

Eji Ogbe tabi Ogbe Meji, Bàbá Odu Ifá

Imagem
  Mo ki yin, olólùfẹ́ èdè ati À ṣ à Yorùbá kaakiri  ni orílẹ̀-èdè  lagbaye. Orúk ọ tèmi ni Adelson Adéwalé de Brito ti ọpọ l ọ́ p ọ̀ ènìyàn m ọ̀ sí Mawo Adelson . Oluk ọ̀ Àgbà èdè ati àṣà Ànàgó ni ìlú Salvador. Olu-ìlú ipinlẹ̀ Baííà ni orílẹ̀-èdè Brasili ìlú Salvador lo n ṣe. M o  fẹ́  kí gbogbo eniyan  máa gbádura si Ọlọ́run pe ki ìjọba r ẹ̀ de laibikita ìsìn olukaluku wọn nitori wipe Ọlọrun nìkan ṣoṣo wa, Ẹ l ẹ́ da naa gbogbo ènìyàn ati Ẹ l ẹ́ da gbogbo ohun to wa ninu ilè Aye. Olùgbàlà wa kí á tó dá ayé, ati nisinsinyii ati títí ayé ainipẹkun, lailai a ṣ ẹ́ . AMIN. Èjì Ogbè  tabi Ogbe Meji, Odu Kini Ifa n ni loni wipe: oju kò kan mi emi kò kan ju ni o difa fún ero pese ti ń l ọ ṣe ọk ọ ìgbín ìgbín ńwá ọk ọ ero pese ńwá ìyàwó àw ọn n mejeeji wá l ọ si ilé alawo ni otootọ ero pese wá bèèrè l ọ́ w ọ́ Ifa wipe nj ẹ́ oun le ni aya ìgbín naa bèèrè l ọ́ w ọ́ alawo r ẹ̀ wipe ńjẹ́ oun le ni ọk ọ awo ń ...

Saudando Exu, o Dono da Força

Imagem
  Meu salve a todos os amantes da língua e cultura iorubá! Meu nome é Professor Adelson Adéwalé de Brito popularmente conhecido como Mawo Adelson. Eu sou um Sacerdote (Líder) líder do Culto aos Voduns, religião que nossos compatriotas africanos trouxeram da costa ocidental da África para as América durante o período que durou a escravidão. Sou cidadão brasileiro, mas tenho orgulho de ser descendente de Anago. Faço parte da geração do povo Anago que foi trazido para este país há trezentos anos, durante o tráfico de escravos. Os Iorubas acreditam que o Todo-Poderoso enviou Ifá do céu para restaurar o mundo com sua Sabedoria. Antigamente, os anciãos Nagô costumavam dizer que antes de pedir qualquer cosa a Ifá, não devemos esquecer de pedir permissão a Exu.... Vamos saudar Exu (Treinem o Oriki original de saudação a Exu Laalu) O Ifa é um Orixá importante para o Culto a Ancestralidade, e é a personificação de um método filosófico para a orientação do modo de vida de cada...